Jóòbù 1:6 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 6 Ó wá di ọjọ́ tí àwọn ọmọ Ọlọ́run tòótọ́*+ ń wọlé láti dúró níwájú Jèhófà,+ Sátánì+ náà sì wọlé sáàárín wọn.+ Jóòbù 38:7 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 7 Nígbà tí àwọn ìràwọ̀ òwúrọ̀+ jọ fayọ̀ ké jáde,Tí gbogbo àwọn ọmọ Ọlọ́run*+ sì bẹ̀rẹ̀ sí í hó yèè, tí wọ́n ń yìn ín? 2 Pétérù 2:4 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 4 Ó dájú pé Ọlọ́run kò fawọ́ sẹ́yìn láti fìyà jẹ àwọn áńgẹ́lì tó ṣẹ̀,+ àmọ́ ó jù wọ́n sínú Tátárọ́sì,*+ ó fi wọ́n sí ìdè* òkùnkùn biribiri de ìdájọ́.+ Júùdù 6 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 6 Ní ti àwọn áńgẹ́lì tó fi ipò wọn àti ibi tó yẹ kí wọ́n máa gbé sílẹ̀,+ ó ti dè wọ́n títí láé sínú òkùnkùn biribiri, ó sì fi wọ́n pa mọ́ de ìdájọ́ ní ọjọ́ ńlá náà.+
6 Ó wá di ọjọ́ tí àwọn ọmọ Ọlọ́run tòótọ́*+ ń wọlé láti dúró níwájú Jèhófà,+ Sátánì+ náà sì wọlé sáàárín wọn.+
7 Nígbà tí àwọn ìràwọ̀ òwúrọ̀+ jọ fayọ̀ ké jáde,Tí gbogbo àwọn ọmọ Ọlọ́run*+ sì bẹ̀rẹ̀ sí í hó yèè, tí wọ́n ń yìn ín?
4 Ó dájú pé Ọlọ́run kò fawọ́ sẹ́yìn láti fìyà jẹ àwọn áńgẹ́lì tó ṣẹ̀,+ àmọ́ ó jù wọ́n sínú Tátárọ́sì,*+ ó fi wọ́n sí ìdè* òkùnkùn biribiri de ìdájọ́.+
6 Ní ti àwọn áńgẹ́lì tó fi ipò wọn àti ibi tó yẹ kí wọ́n máa gbé sílẹ̀,+ ó ti dè wọ́n títí láé sínú òkùnkùn biribiri, ó sì fi wọ́n pa mọ́ de ìdájọ́ ní ọjọ́ ńlá náà.+