-
Jẹ́nẹ́sísì 32:9, 10Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
9 Lẹ́yìn náà, Jékọ́bù sọ pé: “Ọlọ́run Ábúráhámù bàbá mi àti Ọlọ́run Ísákì bàbá mi, Jèhófà, ìwọ tí ò ń sọ fún mi pé, ‘Pa dà sí ilẹ̀ rẹ àti sọ́dọ̀ àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ, màá sì ṣe dáadáa sí ọ,’+ 10 ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ tí o fi hàn àti bí o ṣe jẹ́ olóòótọ́ sí ìránṣẹ́+ rẹ kò tọ́ sí mi, mi ò ní ju ọ̀pá kan ṣoṣo nígbà tí mo sọdá odò Jọ́dánì, àmọ́ mo ti wá di àgọ́ méjì+ báyìí.
-