- 
	                        
            
            2 Sámúẹ́lì 6:18Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        18 Nígbà tí Dáfídì parí rírú àwọn ẹbọ sísun àti àwọn ẹbọ ìrẹ́pọ̀ náà, ó fi orúkọ Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun súre fún àwọn èèyàn náà. 
 
- 
                                        
- 
	                        
            
            2 Kíróníkà 6:3Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        3 Lẹ́yìn náà, ọba yíjú pa dà, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í súre fún gbogbo ìjọ Ísírẹ́lì, bí gbogbo ìjọ Ísírẹ́lì ṣe wà ní ìdúró.+ 
 
-