- 
	                        
            
            Léfítíkù 7:29-31Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        29 “Sọ fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì pé, ‘Kí ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ mú ẹbọ ìrẹ́pọ̀ wá fún Jèhófà mú ọrẹ wá fún Jèhófà látinú ẹbọ ìrẹ́pọ̀ rẹ̀.+ 30 Ọwọ́ ara rẹ̀ ni kó fi mú ọ̀rá+ pẹ̀lú igẹ̀ wá láti fi ṣe ọrẹ àfinásun sí Jèhófà, kó sì fì í síwá-sẹ́yìn bí ọrẹ fífì+ níwájú Jèhófà. 31 Kí àlùfáà mú kí ọ̀rá náà rú èéfín lórí pẹpẹ,+ àmọ́ igẹ̀ náà jẹ́ ti Áárónì àti àwọn ọmọ rẹ̀.+ 
 
-