26 “‘“Èmi yóò bá wọn dá májẹ̀mú àlàáfíà;+ májẹ̀mú ayérayé ni màá bá wọn dá. Èmi yóò gbé wọn kalẹ̀, màá sọ wọ́n di púpọ̀,+ màá sì fi ibi mímọ́ mi sí àárín wọn títí láé.
3 Ni mo bá gbọ́ ohùn kan tó dún ketekete látorí ìtẹ́ náà, ó sọ pé: “Wò ó! Àgọ́ Ọlọ́run wà pẹ̀lú aráyé, á máa bá wọn gbé, wọ́n á sì jẹ́ èèyàn rẹ̀. Ọlọ́run fúnra rẹ̀ máa wà pẹ̀lú wọn.+