- 
	                        
            
            Nọ́ńbà 11:1Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        11 Àwọn èèyàn náà bá bẹ̀rẹ̀ sí í ráhùn gidigidi níwájú Jèhófà. Nígbà tí Jèhófà gbọ́, inú bí i gan-an, iná sì wá látọ̀dọ̀ Jèhófà, ó jó àwọn kan tó wà ní ìkángun ibùdó náà run. 
 
-