- 
	                        
            
            Nọ́ńbà 22:35Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        35 Àmọ́ áńgẹ́lì Jèhófà sọ fún Báláámù pé: “Máa tẹ̀ lé àwọn ọkùnrin náà lọ, àmọ́ ohun tí mo bá sọ fún ọ nìkan ni kí o sọ.” Báláámù wá ń bá àwọn ìjòyè Bálákì lọ. 
 
- 
                                        
- 
	                        
            
            Nọ́ńbà 23:5Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        5 Jèhófà fi ọ̀rọ̀ yìí sí Báláámù+ lẹ́nu pé: “Pa dà sọ́dọ̀ Bálákì, ohun tí wàá sì sọ fún un nìyí.” 
 
-