- 
	                        
            
            Nọ́ńbà 22:7Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
- 
                            - 
                                        7 Torí náà, àwọn àgbààgbà Móábù àtàwọn àgbààgbà Mídíánì mú owó ìwoṣẹ́ dání, wọ́n rìnrìn àjò lọ sọ́dọ̀ Báláámù,+ wọ́n sì jíṣẹ́ Bálákì fún un. 
 
-