ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Diutarónómì 21:6-9
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 6 Kí gbogbo àgbààgbà ìlú tó sún mọ́ òkú náà jù wá fọ ọwọ́ wọn+ sórí ọmọ màlúù náà, èyí tí wọ́n ṣẹ́ ọrùn rẹ̀ ní àfonífojì, 7 kí wọ́n sì kéde pé, ‘Ọwọ́ wa kọ́ ló ta ẹ̀jẹ̀ yìí sílẹ̀, ojú wa ò sì rí i nígbà tí wọ́n ta á sílẹ̀. 8 Jèhófà, má ṣe kà á sí àwọn èèyàn rẹ Ísírẹ́lì lọ́rùn, àwọn tí o rà pa dà,+ má sì jẹ́ kí àwọn èèyàn rẹ Ísírẹ́lì jẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ ẹni tí kò mọwọ́ mẹsẹ̀.’+ A ò sì ní ka ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ náà sí wọn lọ́rùn. 9 Èyí lo fi máa mú ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ ẹni tí kò mọwọ́ mẹsẹ̀ kúrò ní àárín rẹ, torí pé o ṣe ohun tó tọ́ lójú Jèhófà.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́