ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 1 Sámúẹ́lì 7:9
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 9 Sámúẹ́lì wá mú ọ̀dọ́ àgùntàn kan tó ṣì ń mu ọmú, ó sì fi rú odindi ẹbọ sísun+ sí Jèhófà; Sámúẹ́lì ké pe Jèhófà pé kó ran Ísírẹ́lì lọ́wọ́, Jèhófà sì dá a lóhùn.+

  • 1 Sámúẹ́lì 10:8
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 8 Lẹ́yìn náà, lọ sí Gílígálì+ kí n tó dé, màá sì wá bá ọ níbẹ̀ láti rú àwọn ẹbọ sísun àti àwọn ẹbọ ìrẹ́pọ̀. Ọjọ́ méje ni kí o fi dúró títí màá fi wá bá ọ. Ìgbà yẹn ni màá jẹ́ kí o mọ ohun ti wàá ṣe.”

  • 1 Kíróníkà 21:26
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 26 Dáfídì mọ pẹpẹ kan+ síbẹ̀ fún Jèhófà, ó sì rú àwọn ẹbọ sísun àti àwọn ẹbọ ìrẹ́pọ̀, ó ké pe Jèhófà, ẹni tó wá fi iná dá a lóhùn+ láti ọ̀run sórí pẹpẹ ẹbọ sísun náà.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́