2 Àwọn Ọba 10:32 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 32 Lákòókò yẹn, Jèhófà bẹ̀rẹ̀ sí í gé* ìpínlẹ̀ Ísírẹ́lì kù. Hásáẹ́lì ń kọ lù wọ́n léraléra káàkiri ìpínlẹ̀ Ísírẹ́lì,+ 2 Àwọn Ọba 12:17 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 17 Ìgbà náà ni Hásáẹ́lì+ ọba Síríà lọ bá Gátì+ jà, ó sì gbà á, lẹ́yìn náà ó pinnu láti gbéjà ko Jerúsálẹ́mù.*+ 2 Àwọn Ọba 13:3 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 3 Torí náà, ìbínú Jèhófà+ ru sí Ísírẹ́lì,+ ó sì fi wọ́n lé ọwọ́ Hásáẹ́lì+ ọba Síríà àti Bẹni-hádádì+ ọmọ Hásáẹ́lì ní gbogbo ìgbà náà. Émọ́sì 1:3 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 3 “Ohun tí Jèhófà sọ nìyí,‘“Nítorí ìdìtẹ̀* mẹ́ta Damásíkù àti nítorí mẹ́rin, mi ò ní yí ọwọ́ mi pa dà,Nítorí wọ́n fi ohun èlò ìpakà onírin pa Gílíádì bí ọkà.+
32 Lákòókò yẹn, Jèhófà bẹ̀rẹ̀ sí í gé* ìpínlẹ̀ Ísírẹ́lì kù. Hásáẹ́lì ń kọ lù wọ́n léraléra káàkiri ìpínlẹ̀ Ísírẹ́lì,+
17 Ìgbà náà ni Hásáẹ́lì+ ọba Síríà lọ bá Gátì+ jà, ó sì gbà á, lẹ́yìn náà ó pinnu láti gbéjà ko Jerúsálẹ́mù.*+
3 Torí náà, ìbínú Jèhófà+ ru sí Ísírẹ́lì,+ ó sì fi wọ́n lé ọwọ́ Hásáẹ́lì+ ọba Síríà àti Bẹni-hádádì+ ọmọ Hásáẹ́lì ní gbogbo ìgbà náà.
3 “Ohun tí Jèhófà sọ nìyí,‘“Nítorí ìdìtẹ̀* mẹ́ta Damásíkù àti nítorí mẹ́rin, mi ò ní yí ọwọ́ mi pa dà,Nítorí wọ́n fi ohun èlò ìpakà onírin pa Gílíádì bí ọkà.+