-
Jóòbù 1:19, 20Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
19 Ni ìjì tó lágbára bá fẹ́ wá lójijì láti aginjù, ó fẹ́ lu igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ilé náà, ilé náà sì wó lu àwọn ọmọ náà, wọ́n sì kú. Èmi nìkan ló yè bọ́, tí mo sì wá sọ fún ọ.”
20 Ni Jóòbù bá dìde, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó gé irun orí rẹ̀; ó wólẹ̀, ó sì forí balẹ̀,
-