-
2 Kíróníkà 21:16, 17Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
16 Lẹ́yìn náà, Jèhófà gbé+ àwọn Filísínì*+ àti àwọn ará Arébíà+ tó wà nítòsí àwọn ará Etiópíà dìde sí Jèhórámù. 17 Nítorí náà, wọ́n ya bo Júdà, wọ́n sì fi ipá wọ inú rẹ̀, wọ́n kó gbogbo ohun ìní tó wà nínú ilé* ọba,+ wọ́n tún kó àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìyàwó rẹ̀; ọmọ kan ṣoṣo tó ṣẹ́ kù fún un ni Jèhóáhásì,*+ àbíkẹ́yìn rẹ̀.
-