12 Serubábélì+ ọmọ Ṣéálítíẹ́lì+ àti Jóṣúà ọmọ Jèhósádákì,+ àlùfáà àgbà àti gbogbo àwọn tó ṣẹ́ kù nínú àwọn èèyàn náà fetí sí ohùn Jèhófà Ọlọ́run wọn àti sí ọ̀rọ̀ wòlíì Hágáì, torí Jèhófà Ọlọ́run wọn ló rán an; àwọn èèyàn náà sì bẹ̀rẹ̀ sí í bẹ̀rù Jèhófà.