-
Léfítíkù 22:2, 3Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
2 “Sọ fún Áárónì àti àwọn ọmọ rẹ̀ pé kí wọ́n kíyè sára pẹ̀lú bí wọ́n á ṣe máa ṣe* ohun mímọ́ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì, kí wọ́n má sì fi àwọn ohun tí wọ́n ń yà sí mímọ́ fún mi+ sọ orúkọ mímọ́+ mi di aláìmọ́. Èmi ni Jèhófà. 3 Sọ fún wọn pé, ‘Jálẹ̀ àwọn ìran yín, èyíkéyìí nínú àwọn ọmọ yín tó bá ṣì jẹ́ aláìmọ́, tó wá sún mọ́ àwọn ohun mímọ́ tí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì yà sí mímọ́ fún Jèhófà, kí ẹ pa ẹni* náà kúrò níwájú mi.+ Èmi ni Jèhófà.
-