ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 49:6, 7
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  6 Àwọn tí wọ́n gbẹ́kẹ̀ lé ọrọ̀ wọn,+

      Tí wọ́n sì ń fi ọrọ̀ rẹpẹtẹ wọn fọ́nnu,+

       7 Kò sí ìkankan nínú wọn tó lè ra arákùnrin kan pa dà

      Tàbí tí ó lè fún Ọlọ́run ní ìràpadà nítorí rẹ̀,+

  • Òwe 11:4
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  4 Ọrọ̀* kò ní ṣeni láǹfààní ní ọjọ́ ìbínú ńlá,+

      Àmọ́ òdodo ló ń gbani lọ́wọ́ ikú.+

  • Jeremáyà 9:23
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 23 Ohun tí Jèhófà sọ nìyí:

      “Kí ọlọ́gbọ́n má ṣe yangàn nítorí ọgbọ́n rẹ̀;+

      Kí alágbára má ṣe yangàn nítorí agbára rẹ̀;

      Kí ọlọ́rọ̀ má sì yangàn nítorí ọrọ̀ rẹ̀.”+

  • Lúùkù 12:19-21
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 19 màá sì sọ fún ara* mi pé: “O ní* ọ̀pọ̀ nǹkan rere tí mo ti tò jọ fún ọ̀pọ̀ ọdún; fọkàn balẹ̀, máa jẹ, máa mu, máa gbádùn ara ẹ.”’ 20 Àmọ́ Ọlọ́run sọ fún un pé, ‘Aláìlóye, òru òní ni wọ́n máa béèrè ẹ̀mí* rẹ lọ́wọ́ rẹ. Ta ló máa wá ni àwọn ohun tí o ti tò jọ?’+ 21 Bẹ́ẹ̀ ló máa rí fún ẹni tó bá ń to ìṣúra jọ fún ara rẹ̀ àmọ́ tí kò ní ọrọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run.”+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́