-
Nọ́ńbà 31:50Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
50 Torí náà, jẹ́ kí ẹnì kọ̀ọ̀kan wa mú ohun tó rí wá láti fi ṣe ọrẹ fún Jèhófà, ìyẹn àwọn ohun tí wọ́n fi wúrà ṣe, ẹ̀gbà ẹsẹ̀, ẹ̀gbà ọwọ́, òrùka àṣẹ, yẹtí àtàwọn ohun ọ̀ṣọ́ míì, láti fi ṣe ètùtù fún ara* wa níwájú Jèhófà.”
-