Àìsáyà 60:14 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 14 Àwọn ọmọ àwọn tó fìyà jẹ ọ́ máa wá, wọ́n á sì tẹrí ba níwájú rẹ;Gbogbo àwọn tó ń hùwà àfojúdi sí ọ gbọ́dọ̀ tẹrí ba níbi ẹsẹ̀ rẹ,Wọ́n sì máa pè ọ́ ní ìlú Jèhófà,Síónì Ẹni Mímọ́ Ísírẹ́lì.+ Jeremáyà 31:33 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 33 “Nítorí májẹ̀mú tí màá bá ilé Ísírẹ́lì dá lẹ́yìn ìgbà yẹn nìyí,” ni Jèhófà wí. “Màá fi òfin mi sínú wọn,+ inú ọkàn wọn sì ni màá kọ ọ́ sí.+ Màá di Ọlọ́run wọn, wọ́n á sì di èèyàn mi.”+ Sekaráyà 8:8 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 8 Èmi yóò mú wọn wá, wọn yóò sì máa gbé ní Jerúsálẹ́mù;+ wọn yóò di èèyàn mi, èmi yóò sì di Ọlọ́run wọn+ ní òtítọ́ àti ní òdodo.’”
14 Àwọn ọmọ àwọn tó fìyà jẹ ọ́ máa wá, wọ́n á sì tẹrí ba níwájú rẹ;Gbogbo àwọn tó ń hùwà àfojúdi sí ọ gbọ́dọ̀ tẹrí ba níbi ẹsẹ̀ rẹ,Wọ́n sì máa pè ọ́ ní ìlú Jèhófà,Síónì Ẹni Mímọ́ Ísírẹ́lì.+
33 “Nítorí májẹ̀mú tí màá bá ilé Ísírẹ́lì dá lẹ́yìn ìgbà yẹn nìyí,” ni Jèhófà wí. “Màá fi òfin mi sínú wọn,+ inú ọkàn wọn sì ni màá kọ ọ́ sí.+ Màá di Ọlọ́run wọn, wọ́n á sì di èèyàn mi.”+
8 Èmi yóò mú wọn wá, wọn yóò sì máa gbé ní Jerúsálẹ́mù;+ wọn yóò di èèyàn mi, èmi yóò sì di Ọlọ́run wọn+ ní òtítọ́ àti ní òdodo.’”