Léfítíkù 26:31 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 31 Èmi yóò mú kí idà pa àwọn ìlú yín,+ màá sì sọ àwọn ibi mímọ́ yín di ahoro, mi ò ní gbọ́ òórùn dídùn* àwọn ẹbọ yín. Àìsáyà 1:11 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 11 “Àǹfààní wo ni ọ̀pọ̀ ẹbọ yín ń ṣe mí?”+ ni Jèhófà wí. “Àwọn ẹbọ sísun yín tí ẹ fi àgbò+ ṣe àti ọ̀rá àwọn ẹran tí ẹ bọ́ dáadáa + ti sú mi,Inú mi ò dùn sí ẹ̀jẹ̀+ àwọn akọ ọmọ màlúù,+ ọ̀dọ́ àgùntàn àti ewúrẹ́.+ Jeremáyà 15:1 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 15 Nígbà náà, Jèhófà sọ fún mi pé: “Bí Mósè àti Sámúẹ́lì bá tiẹ̀ dúró níwájú mi,+ mi ò ní ṣojúure sí* àwọn èèyàn yìí. Lé wọn kúrò níwájú mi, kí wọ́n máa lọ. Ìsíkíẹ́lì 24:13 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 13 “‘Ìwà àìnítìjú rẹ ló mú kí o di aláìmọ́.+ Mo wẹ̀ ọ́ títí kí o lè mọ́, àmọ́ ìwà àìmọ́ rẹ kò kúrò. Ìwọ kì yóò mọ́ títí ìbínú mi sí ọ fi máa rọlẹ̀.+
31 Èmi yóò mú kí idà pa àwọn ìlú yín,+ màá sì sọ àwọn ibi mímọ́ yín di ahoro, mi ò ní gbọ́ òórùn dídùn* àwọn ẹbọ yín.
11 “Àǹfààní wo ni ọ̀pọ̀ ẹbọ yín ń ṣe mí?”+ ni Jèhófà wí. “Àwọn ẹbọ sísun yín tí ẹ fi àgbò+ ṣe àti ọ̀rá àwọn ẹran tí ẹ bọ́ dáadáa + ti sú mi,Inú mi ò dùn sí ẹ̀jẹ̀+ àwọn akọ ọmọ màlúù,+ ọ̀dọ́ àgùntàn àti ewúrẹ́.+
15 Nígbà náà, Jèhófà sọ fún mi pé: “Bí Mósè àti Sámúẹ́lì bá tiẹ̀ dúró níwájú mi,+ mi ò ní ṣojúure sí* àwọn èèyàn yìí. Lé wọn kúrò níwájú mi, kí wọ́n máa lọ.
13 “‘Ìwà àìnítìjú rẹ ló mú kí o di aláìmọ́.+ Mo wẹ̀ ọ́ títí kí o lè mọ́, àmọ́ ìwà àìmọ́ rẹ kò kúrò. Ìwọ kì yóò mọ́ títí ìbínú mi sí ọ fi máa rọlẹ̀.+