-
Sefanáyà 2:9, 10Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
9 Nítorí náà, bí mo ti wà láàyè,” ni Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun, Ọlọ́run Ísírẹ́lì wí,
“Móábù máa dà bíi Sódómù gẹ́lẹ́,+
Àti àwọn ọmọ Ámónì bíi Gòmórà,+
Ibi tí èsìsì wà, tí kòtò iyọ̀ wà, tó sì ti di ahoro títí láé.+
Àwọn tó ṣẹ́ kù lára àwọn èèyàn mi á kó wọn lọ,
Àwọn tó ṣẹ́ kù nínú orílẹ̀-èdè mi á sì gba tọwọ́ wọn.
10 Èyí ni ohun tí wọ́n máa gbà nítorí ìgbéraga wọn,+
Torí pé wọ́n kẹ́gàn, wọ́n sì ń gbé ara wọn ga sí àwọn èèyàn Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun.
-