ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jóẹ́lì 3:4-6
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  4 Kí ló dé tí ẹ fi ṣe báyìí sí mi,

      Tírè, Sídónì àti gbogbo ilẹ̀ Filísíà?

      Ṣé mo ṣẹ̀ yín ni tí ẹ fi ń gbẹ̀san?

      Tó bá jẹ́ ẹ̀san lẹ̀ ń gbà,

      Ṣe ni màá yára dá a pa dà sórí yín láìjáfara.+

       5 Torí ẹ ti kó fàdákà àti wúrà mi,+

      Ẹ sì ti kó àwọn ìṣúra mi tó ṣeyebíye gan-an lọ sínú àwọn tẹ́ńpìlì yín;

       6 Ẹ ti ta àwọn èèyàn Júdà àti Jerúsálẹ́mù fún àwọn Gíríìkì,+

      Kí ẹ lè lé wọn jìnnà kúrò ní ilẹ̀ wọn;

  • Émọ́sì 1:9
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  9 Ohun tí Jèhófà sọ nìyí,

      ‘Nítorí ìdìtẹ̀ mẹ́ta Tírè+ àti nítorí mẹ́rin, mi ò ní yí ọwọ́ mi pa dà,

      Nítorí wọ́n kó gbogbo àwọn tí wọ́n mú nígbèkùn, wọ́n sì fà wọ́n lé Édómù lọ́wọ́,

      Àti nítorí pé wọn kò rántí májẹ̀mú àwọn arákùnrin.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́