Míkà 7:6 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 6 Torí ọmọkùnrin ń tàbùkù sí bàbá rẹ̀,Ọmọbìnrin ń bá ìyá rẹ̀ jà,+Ìyàwó ń gbógun ti ìyá ọkọ rẹ̀;+Ará ilé ẹni ni ọ̀tá ẹni.+ Mátíù 10:21 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 21 Bákan náà, arákùnrin máa fa arákùnrin lé ikú lọ́wọ́, bàbá máa ṣe bẹ́ẹ̀ sí ọmọ rẹ̀, àwọn ọmọ máa dìde sí àwọn òbí, wọ́n sì máa pa wọ́n.+ Lúùkù 21:16 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 16 Bákan náà, àwọn òbí, àwọn arákùnrin, àwọn mọ̀lẹ́bí àti àwọn ọ̀rẹ́ pàápàá máa fà yín léni lọ́wọ́,* wọ́n máa pa àwọn kan nínú yín,+ 2 Tímótì 3:1 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 3 Àmọ́ kí o mọ èyí pé, àwọn ọjọ́ ìkẹyìn+ yóò jẹ́ àkókò tí nǹkan máa le gan-an, tó sì máa nira. 2 Tímótì 3:3 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 3 ẹni tí kò ní ìfẹ́ àdámọ́ni, kìígbọ́-kìígbà,* abanijẹ́, ẹni tí kò lè kó ara rẹ̀ níjàánu, ẹni tó burú gan-an, ẹni tí kò nífẹ̀ẹ́ ohun rere,
6 Torí ọmọkùnrin ń tàbùkù sí bàbá rẹ̀,Ọmọbìnrin ń bá ìyá rẹ̀ jà,+Ìyàwó ń gbógun ti ìyá ọkọ rẹ̀;+Ará ilé ẹni ni ọ̀tá ẹni.+
21 Bákan náà, arákùnrin máa fa arákùnrin lé ikú lọ́wọ́, bàbá máa ṣe bẹ́ẹ̀ sí ọmọ rẹ̀, àwọn ọmọ máa dìde sí àwọn òbí, wọ́n sì máa pa wọ́n.+
16 Bákan náà, àwọn òbí, àwọn arákùnrin, àwọn mọ̀lẹ́bí àti àwọn ọ̀rẹ́ pàápàá máa fà yín léni lọ́wọ́,* wọ́n máa pa àwọn kan nínú yín,+
3 ẹni tí kò ní ìfẹ́ àdámọ́ni, kìígbọ́-kìígbà,* abanijẹ́, ẹni tí kò lè kó ara rẹ̀ níjàánu, ẹni tó burú gan-an, ẹni tí kò nífẹ̀ẹ́ ohun rere,