ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sefanáyà

SEFANÁYÀ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Ọjọ́ ìdájọ́ Jèhófà ti sún mọ́lé (1-18)

      • Ọjọ́ Jèhófà ń yára bọ̀ kánkán (14)

      • Fàdákà àti wúrà kò ní lè gba àwọn èèyàn là (18)

  • 2

    • Ẹ wá Jèhófà kí ọjọ́ ìbínú rẹ̀ tó dé (1-3)

      • Ẹ wá òdodo àti ìwà pẹ̀lẹ́ (3)

      • “Bóyá ẹ ó rí ààbò” (3)

    • Ìdájọ́ lórí àwọn orílẹ̀-èdè tó yí wọn ká (4-15)

  • 3

    • Jerúsálẹ́mù, ìlú tí ọ̀tẹ̀ àti ìwàkiwà kún inú rẹ̀ (1-7)

    • Ìdájọ́ àti ìpadàbọ̀sípò (8-20)

      • Ìyípadà sí èdè mímọ́ (9)

      • A ó gba àwọn onírẹ̀lẹ̀ àtàwọn aláìní là (12)

      • Jèhófà máa yọ̀ nítorí Síónì (17)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́