MÁTÍÙ
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
-
ÀWỌN ÀPÈJÚWE NÍPA ÌJỌBA NÁÀ (1-52)
Afúnrúgbìn (1-9)
Ìdí tí Jésù fi lo àwọn àpèjúwe (10-17)
Ó sọ ìtumọ̀ àpèjúwe afúnrúgbìn (18-23)
Àlìkámà àti èpò (24-30)
Hóró músítádì àti ìwúkàrà (31-33)
Bó ṣe lo àwọn àpèjúwe mú àsọtẹ́lẹ̀ ṣẹ (34, 35)
Ó sọ ìtumọ̀ àpèjúwe àlìkámà àti èpò (36-43)
Ìṣúra tó pa mọ́ àti péálì tó dáa (44-46)
Àwọ̀n (47-50)
Ìṣúra tuntun àti ti àtijọ́ (51, 52)
Wọn ò gba Jésù ní agbègbè ìlú rẹ̀ (53-58)
-
Àwọn àlùfáà gbìmọ̀ pọ̀ láti pa Jésù (1-5)
Ó da òróró onílọ́fínńdà sára Jésù (6-13)
Ìrékọjá tó gbẹ̀yìn àti ẹni tó máa da Jésù (14-25)
Jésù fi Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa lọ́lẹ̀ (26-30)
Ó sọ tẹ́lẹ̀ pé Pétérù máa sẹ́ òun (31-35)
Jésù gbàdúrà ní Gẹ́tísémánì (36-46)
Wọ́n mú Jésù (47-56)
Wọ́n gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ níwájú Sàhẹ́ndìrìn (57-68)
Pétérù sẹ́ Jésù (69-75)