-   1   Àwọn Ànímọ́ Jèhófà 
-   2   A Dúpẹ́ Lọ́wọ́ Rẹ Jèhófà 
-   3   “Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́” 
-   4   Bá A Ṣe Lè Ní Orúkọ Rere Lọ́dọ̀ Ọlọ́run 
-   5   Kristi, Àwòfiṣàpẹẹrẹ Wa 
-   6   Àdúrà Ìránṣẹ́ Ọlọ́run 
-   7   Ìyàsímímọ́ Kristẹni 
-   8   Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa 
-   9   Ẹ Yin Jèhófà, Ọlọ́run Wa! 
-  10   “Èmi Nìyí! Rán Mi” 
-  11   Mímú Ọkàn Jèhófà Yọ̀ 
-  12   Ọlọ́run Ṣèlérí Ìyè Àìnípẹ̀kun 
-  13   Àdúrà Ìdúpẹ́ 
-  14   Jèhófà Sọ Ohun Gbogbo Di Tuntun 
-  15   Ìṣẹ̀dá Ń Ṣí Ògo Jèhófà Payá 
-  16   Ẹ Sá Wá Sábẹ́ Ìjọba Ọlọ́run! 
-  17   Ẹ Tẹ̀ Síwájú Ẹ̀yin Ẹlẹ́rìí! 
-  18   Ìfẹ́ Ọlọ́run Tó Dúró Ṣinṣin 
-  19   Ọlọ́run Ṣèlérí Párádísè 
-  20   Bù Kún Ìpéjọ Wa 
-  21   Aláyọ̀ Ni Àwọn Aláàánú! 
-  22   “Jèhófà Ni Olùṣọ́ Àgùntàn Mi” 
-  23   Jèhófà, Okun Wa 
-  24   Tẹjú Mọ́ Èrè Náà! 
-  25   Ẹ̀rí Tó Fi Hàn Pé Ọmọ Ẹ̀yìn Kristi Ni Wá 
-  26   Bá Ọlọ́run Rìn! 
-  27   Dúró Sọ́dọ̀ Jèhófà! 
-  28   Orin Tuntun 
-  29   Rírìn Nínú Ìwà Títọ́ 
-  30   Jèhófà Bẹ̀rẹ̀ Ìṣàkóso Rẹ̀ 
-  31   Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ni Wá! 
-  32   Ẹ Fẹsẹ̀ Múlẹ̀ Ṣinṣin! 
-  33   Ẹ Má Bẹ̀rù Wọn! 
-  34   Jíjẹ́ Kí Orúkọ Wa Máa Rò Wá 
-  35   Ọpẹ́ fún Sùúrù Ọlọ́run 
-  36   “Ohun Tí Ọlọ́rùn Ti So Pọ̀” 
-  37   Ọlọ́run Mí sí Ìwé Mímọ́ 
-  38   Ju Ẹrù Ìnira Rẹ Sọ́dọ̀ Jèhófà 
-  39   Àlàáfíà Tó Wà Láàárín Wa 
-  40   Ẹ Máa Wá Ìjọba Náà Lákọ̀ọ́kọ́ 
-  41   Sin Jèhófà Nígbà Èwe 
-  42   “Ṣèrànwọ́ fún Àwọn Tí  Wọ́n Jẹ́ Aláìlera” 
-  43   Ẹ Wà Lójúfò,  Ẹ Dúró Gbọn-in, Ẹ Di Alágbára 
-  44   Máa Fìdùnnú Kópa Nínú Ìkórè Náà 
-  45   Ẹ Máa Tẹ̀ Síwájú! 
-  46   Jèhófà Ni Ọba Wa! 
-  47   Polongo Ìhìn Rere 
-  48   Bíbá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́ 
-  49   Jèhófà Ni Ibi Ìsádi Wa 
-  50   Àpẹẹrẹ Ìfẹ́ Ọlọ́run 
-  51   A Rọ̀ Mọ́ Jèhófà 
-  52   Máa Ṣọ́ Ọkàn Rẹ 
-  53   Ṣíṣiṣẹ́ Pa Pọ̀ ní Ìṣọ̀kan 
-  54   A Ní Láti Nígbàgbọ́ 
-  55   Ìyè Àìnípẹ̀kun Nígbẹ̀yìngbẹ́yín! 
-  56   Jọ̀wọ́ Gbọ́ Àdúrà Mi 
-  57   Àṣàrò Ọkàn Mi 
-  58   Àdúrà Ìyàsímímọ́ Mi 
-  59   Ọlọ́run Ni A Ya Ara  Wa sí Mímọ́ Fún! 
-  60   Yóò Sọ Ọ́ Di Alágbára 
-  61   Irú Ènìyàn Tó Yẹ Kí N Jẹ́ 
-  62   Ti Ta Ni Àwa Jẹ́? 
-  63   Jẹ́ Adúróṣinṣin 
-  64   Sọ Òtítọ́ Di Tìrẹ 
-  65   “Èyí Ni Ọ̀nà” 
-  66   Fífi Gbogbo Ọkàn Sin Jèhófà 
-  67   Máa Gbàdúrà sí Jèhófà Lójoojúmọ́ 
-  68   Àdúrà Ẹni Rírẹlẹ̀ 
-  69   Mú Mi Mọ Àwọn Ọ̀nà Rẹ 
-  70   “Máa Wádìí Dájú Àwọn Ohun Tí Ó Ṣe Pàtàkì Jù” 
-  71   Ẹ̀mí Mímọ́, Ẹ̀bùn Ọlọ́run 
-  72   Bá A Ṣe Lè Ní Ìfẹ́ 
-  73   Ká Nífẹ̀ẹ́ Ara Wa Látọkàn Wá 
-  74   Ìdùnnú Jèhófà 
-  75   Ìdí Ayọ̀ Wa Pọ̀ 
-  76   Jèhófà, Ọlọ́run Àlàáfíà 
-  77   Ẹ Máa Dárí Jini 
-  78   Ìpamọ́ra 
-  79   Agbára Inú Rere 
-  80   Ìwà Rere 
-  81   “Fún Wa Ní Ìgbàgbọ́ Sí I” 
-  82   Jẹ́ Onínú Tútù Bíi Kristi 
-  83   Ó Yẹ Ká Ní Ìkóra-Ẹni-Níjàánu 
-  84   “Mo Fẹ́ Bẹ́ẹ̀” 
-  85   Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ Èrè Látọ̀dọ̀ Jèhófà 
-  86   Àwọn Obìnrin Olóòótọ́, Àwọn Arábìnrin 
-  87   A Ti Di Ọ̀kan Ṣoṣo 
-  88   Ọmọ Jẹ́ Ohun Ìní Tí Ọlọ́run Fi Síkàáwọ́ Òbí 
-  89   Jèhófà Fìfẹ́ Rọ̀ Ọ́ Pé: “Ọmọ Mi, Jẹ́ Ọlọ́gbọ́n” 
-  90   Ẹwà Orí Ewú 
-  91   Baba Mi, Ọlọ́run Mi àti Ọ̀rẹ́ Mi 
-  92   “Wàásù Ọ̀rọ̀ Náà” 
-  93   “Kí Ìmọ́lẹ̀ Yín Máa Tàn” 
-  94   Àwọn Ẹ̀bùn Rere Ọlọ́run Tẹ́ Wa Lọ́rùn 
-  95   “Ẹ Tọ́ Ọ Wò, Kí Ẹ sì Rí I Pé Jèhófà Jẹ́ Ẹni Rere” 
-  96   Ẹ Wá Àwọn Ẹni Yíyẹ Kàn 
-  97   Ẹ Tẹ̀ Síwájú, Ẹ̀yin Òjíṣẹ́ Ìjọba Ọlọ́run! 
-  98   Fífúnrúgbìn Èso Ìjọba Ọlọ́run 
-  99   Ẹ Yin Ọba Tuntun Tó Jẹ Lórí Ayé 
- 100   Ẹgbẹ́ Ọmọ Ogun Jèhófà Ni Wá! 
- 101   Sísọ Òtítọ́ Ìjọba Ọlọ́run Di Mímọ̀ 
- 102   Dara Pọ̀ Nínú  Kíkọ Orin Ìjọba Náà! 
- 103   “Láti Ilé dé Ilé” 
- 104   Ẹ Bá Mi Yin Jáà 
- 105   Àwọn Ọ̀run Ń Polongo Ògo Ọlọ́run 
- 106   Bá A Ṣe Lè Di Ọ̀rẹ́ Jèhófà 
- 107   Wá sí Òkè Jèhófà 
- 108   Ẹ Yin Jèhófà Nítorí Ìjọba Rẹ̀ 
- 109   Yin Àkọ́bí Jèhófà! 
- 110   Àwọn Iṣẹ́ Àgbàyanu Ọlọ́run 
- 111   Òun Yóò Pè 
- 112   Jèhófà, Ọlọ́run Gíga 
- 113   A Dúpẹ́ Lọ́wọ́ Ọlọ́run Nítorí Ọ̀rọ̀ Rẹ̀ 
- 114   Ìwé Ọlọ́run Jẹ́ Ìṣúra 
- 115   Bá A Ṣe Lè Ṣe Ọ̀nà Wa Ní Rere 
- 116   Ìmọ́lẹ̀ Náà Ń Mọ́lẹ̀ Sí I 
- 117   A Gbọ́dọ̀ Kẹ́kọ̀ọ́ Lọ́dọ̀ Jèhófà 
- 118   Ẹ Fìdùnnú Tẹ́wọ́ Gba Ara Yín 
- 119   Ẹ Wá Gba Ìtura! 
- 120   Gbọ́, Ṣègbọràn, Kó O sì Gba Ìbùkún 
- 121   Ká Máa Fún Ara Wa Níṣìírí 
- 122   Ẹgbẹẹgbẹ̀rún Àwa Ará 
- 123   Àwọn Olùṣọ́ Àgùntàn Jẹ́ Ẹ̀bùnn 
- 124   Gbà Wọ́n Pẹ̀lú Ẹ̀mí Aájò Àlejò 
- 125   Fífi Ìdúróṣinṣin Tẹrí Ba fún Ìṣàkóso Ọlọ́run 
- 126   Òpò Tá A Fi Ìfẹ́ Ṣe 
- 127   Ibi Tá A Ń Fi Orúkọ Rẹ Pè 
- 128   Ipò Nǹkan Ń Yí Pa Dà Ní Ayé Yìí 
- 129   Dídi Ìrètí Wa Mú Ṣinṣin 
- 130   Ìyanu Ni Ìwàláàyè Jẹ́ 
- 131   Jèhófà Ń Ṣe Ọ̀nà Àsálà 
- 132   Orin Ìṣẹ́gun 
- 133   Wá Ọlọ́run Kó O Lè Rí Ìgbàlà 
- 134   Fojú Inú Wo Ìgbà Tí Gbogbo Nǹkan Yóò Di Tuntun 
- 135   Fífara Dà Á Dópin