ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • scl ojú ìwé 38-39
  • Ẹ̀rí Ọkàn

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ẹ̀rí Ọkàn
  • Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
scl ojú ìwé 38-39

Ẹ̀rí Ọkàn

Ẹ̀rí wo ló fi hàn pé gbogbo èèyàn ni Jèhófà fún ní ẹ̀rí ọkàn?

Ro 2:14, 15

Tún wo 2Kọ 4:2

Tẹ́nì kan ò bá jáwọ́ nínú ìwà burúkú, kí ló máa ṣẹlẹ̀ sí ẹ̀rí ọkàn ẹ̀?

1Ti 4:2; Tit 1:15

Tún wo Heb 10:22

Tẹ́nì kan bá ṣáà ti gbà pé ohun tó dáa lòun ń ṣe, ṣéyẹn náà ti tó?

Jo 16:2, 3; Ro 10:2, 3

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • 2Kr 18:1-3; 19:1, 2—Jèhófà bínú sí Ọba Jèhóṣáfátì torí pé ó ran Áhábù tó jẹ́ ọba búburú lọ́wọ́

    • Iṣe 22:19, 20; 26:9-11—Àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù sọ pé nígbà kan, òun gbà pé ó dáa bóun ṣe ń ṣenúnibíni sáwọn ọmọ ẹ̀yìn Kristi tóun sì ń fọwọ́ sí i pé kí wọ́n pa wọ́n

Báwo la ṣe lè kọ́ ẹ̀rí ọkàn wa kó lè máa ṣiṣẹ́ dáadáa?

2Ti 3:16, 17; Heb 5:14

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • 1Sa 24:2-7—Torí pé ẹ̀rí ọkàn Ọba Dáfídì ń ṣiṣẹ́ dáadáa, kò hùwà àìdáa sí Ọba Sọ́ọ̀lù tó jẹ́ ẹni àmì òróró Jèhófà

Báwo làwa èèyàn aláìpé ṣe lè ní ẹ̀rí ọkàn tó mọ́ lójú Ọlọ́run?

Ef 1:7; Heb 9:14; 1Pe 3:21; 1Jo 1:7, 9; 2:1, 2

Tún wo Ifi 1:5

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Ais 6:1-8—Jèhófà fi wòlíì Àìsáyà lọ́kàn balẹ̀ pé òun máa dárí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ẹ̀ jì í

    • Ifi 7:9-14—Ẹbọ ìràpadà Jésù ló mú kó ṣeé ṣe fún ogunlọ́gọ̀ èèyàn láti ní àjọṣe tímọ́tímọ́ pẹ̀lú Jèhófà

Kí nìdí tó fi yẹ ká máa hùwà níbàámu pẹ̀lú ẹ̀rí ọkàn wa tá a ti fi Bíbélì kọ́?

Iṣe 24:15, 16; 1Ti 1:5, 6, 19; 1Pe 3:16

Tún wo Ro 13:5

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Jẹ 2:25; 3:6-13—Ádámù àti Éfà ṣàìgbọràn sí Ọlọ́run torí pé wọn ò tẹ̀ lé ẹ̀rí ọkàn wọn, èyí sì kó ìtìjú bá wọn

    • Ne 5:1-13—Nígbà táwọn Júù pa òfin Ọlọ́run tì, tí wọ́n sì ń gba owó èlé tó pọ̀ lọ́wọ́ àwọn èèyàn wọn, Gómìnà Nehemáyà bá wọn sọ̀rọ̀ kí ẹ̀rí ọkàn wọn lè mú kí wọ́n ṣe ohun tó tọ́

Kí nìdí tó fi yẹ ká kíyè sára ká máa bàa kó ẹ̀dùn ọkàn bá arákùnrin tàbí arábìnrin tí ẹ̀rí ọkàn ẹ̀ kò tíì lágbára?

1Kọ 8:7, 10-13; 10:28, 29

Kí ló yẹ ká pinnu nípa ẹ̀rí ọkàn wa?

2Kọ 1:12; 2Ti 1:3; Heb 13:18

Tún wo Iṣe 23:1; Ro 9:1; 1Ti 3:8, 9

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́