ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • scl ojú ìwé 84
  • Ìwà Àìdáa

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ìwà Àìdáa
  • Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
scl ojú ìwé 84

Ìwà Àìdáa

Báwo ló ṣe máa ń rí lára wa táwọn èèyàn bá hùwà àìdáa sí wa?

Sm 69:20; Owe 18:14; Onw 4:1-3; Mal 2:13-16; Kol 3:21

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • 2Sa 10:1-5—Nígbà táwọn ọ̀tá dójú ti àwọn kan lára àwọn ọmọ ogun Ọba Dáfídì, ó fi inúure hàn sí wọn

    • 2Sa 13:6-19—Támárì sunkún, ó sì fa aṣọ ara ẹ̀ ya lẹ́yìn tí Ámínónì fipá bá a lò pọ̀, tó dojú tì í, tó sì lé e jáde

Tí wọ́n bá hùwà àìdáa sẹ́nì kan, báwo la ṣe mọ̀ pé Jèhófà mọ gbogbo ohun tó ṣẹlẹ̀, kí ló sì máa ṣe nípa ẹ̀?

Job 34:21, 22; Sm 37:8, 9; Ais 29:15, 19-21; Ro 12:17-21

Tún wo Sm 63:6, 7

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • 1Sa 25:3, 14-17, 21, 32-38—Nábálì sọ̀rọ̀ burúkú sí Ọba Dáfídì, èyí sì fi ẹ̀mí àwọn ará ilé ẹ̀ sínú ewu. Nígbà tó yá, Jèhófà fìyà jẹ Nábálì, ó sì kú

    • Jer 20:1-6, 9, 11-13—Jeremáyà kọ́kọ́ rẹ̀wẹ̀sì nígbà tí àlùfáà kan tó ń jẹ́ Páṣúrì lù ú, tó sì fi í sínú àbà; lẹ́yìn náà, Jèhófà fún Jeremáyà lókun, ó sì gbà á sílẹ̀

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́