ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • scl ojú ìwé 49-50
  • Ìfòyebánilò

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ìfòyebánilò
  • Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
Àwọn Ẹsẹ Bíbélì Tó Lè Ran Àwa Kristẹni Lọ́wọ́
scl ojú ìwé 49-50

Ìfòyebánilò

Kí nìdí tó fi yẹ káwa Kristẹni máa fòye báni lò?

Flp 4:5; Tit 3:2; Jem 3:17

Tún wo 1Ti 3:2, 3

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Jẹ 18:23-33—Jèhófà ní sùúrù fún Ábúráhámù nígbà tó ń bi í ní ìbéèrè nípa ìparun Sódómù àti Gòmórà

    • Jẹ 19:16-22, 30—Lọ́ọ̀tì ní kí Jèhófà jẹ́ kóun sá lọ sí Sóárì dípò tóun á fi sá lọ sí agbègbè olókè, Jèhófà sì gbà kó ṣe bẹ́ẹ̀ torí pé Jèhófà máa ń fòye báni lò

    • Mt 15:21-28—Jésù fi hàn pé òun máa ń fòye báni lò, ó ṣe ohun tí obìnrin ará Foníṣíà kan béèrè nígbà tó rí i pé obìnrin náà ní ìgbàgbọ́ tó lágbára

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́