ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 August ojú ìwé 2
  • August 7-13

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • August 7-13
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 August ojú ìwé 2

August 7-13

Ìsíkíẹ́lì 28-31

  • Orin 85 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Jèhófà San Ìlú Abọ̀rìṣà Kan Lẹ́san”: (10 min.)

    • Isk 29:18​—⁠Nebukadinésárì ọba Bábílónì kò gba èrè kankan fún bó ṣe ṣẹ́gun ìlú Tírè (it-2 1136 ¶4)

    • Isk 29:19​—⁠Ọba Nebukadinésárì gba Íjíbítì gẹ́gẹ́ bí ohun ìfiṣèjẹ dípò Tírè (it-1 698 ¶5)

    • Isk 29:20​—⁠Jèhófà san àwọn ará Bábílónì lẹ́san torí pé wọ́n ṣe ohun tó bá ìfẹ́ rẹ̀ mu (g86 11/⁠8 27 ¶4-5)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Isk 28:​12-19​—⁠Báwo ni ìwà tí àwọn alákòóso ìlú Tírè hù ṣe jọ irú ìwà tí Sátánì hù? (it-2 604 ¶4-5)

    • Isk 30:​13, 14​—⁠Báwo ni àsọtẹ́lẹ̀ yìí ṣe ní ìmúṣẹ? (w03 7/⁠1 32 ¶1-3)

    • Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Isk 29:​1-12

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Múra Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Oṣù Yìí Sílẹ̀: (15 min.) Ìjíròrò tó dá lórí “Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò.” Jẹ́ kí àwọn ará wo ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn fídíò ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀, kẹ́ ẹ sì jíròrò àwọn kókó pàtàkì látinú àwọn fídíò náà. Gba àwọn ará níyànjú pé kí wọ́n mẹ́nu ba àwọn nǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ lákòókò tá a wà yìí tí wọ́n bá ń gbé ọ̀rọ̀ wọn kalẹ̀, kí wọ́n sì lo fídíò náà Ṣé O Fẹ́ Gbọ́ Ìròyìn Ayọ̀? nígbà tí wọ́n bá ń fi ìwé Ìròyìn Ayọ̀ lọni.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 82

  • Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ: (5 min.) Tàbí kẹ́ ẹ jíròrò ohun tẹ́ ẹ rí kọ́ nínú Ìwé Ọdọọdún. (yb17 35-36 áti Àpótí tó wà ní ojú ìwé 35)

  • “Àwọn Ànímọ́ Kristẹni Tó Yẹ Kó O Ní​—⁠Ìrẹ̀lẹ̀”: (10 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà Yẹra fún Ohun Tó Lè Ba Ìdúróṣinṣin Rẹ Jẹ́​—⁠Ìgbéraga.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) kr “Apá 5​—Ètò Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Ìjọba Ọlọ́run—Bí Àwọn Ìránṣẹ́ Ọba Náà Ṣe Ń Gba Ìdálẹ́kọ̀ọ́, orí 16 1-5, àwọn àpótí “Ìjọsìn Ìdílé” áti “Àwọn Àpéjọ Ọdọọdún Tó Ń Mú Káwọn Èèyàn Ọlọ́run Wà Níṣọ̀kan”

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 20 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́