ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb19 September ojú ìwé 6
  • September 30–October 6

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • September 30–October 6
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
mwb19 September ojú ìwé 6

September 30–October 6

JÉMÍÌSÌ 1-2

  • Orin 122 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Ohun Tó Ń Fa Ẹ̀ṣẹ̀ àti Ikú”: (10 min.)

    • [Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jémíìsì.]

    • Jem 1:14​—Èròkerò máa ń mú kí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ jọba lọ́kàn ẹni (g17.4 14)

    • Jem 1:15​—Ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ máa ń mú kéèyàn dẹ́ṣẹ̀, ìyẹn sì máa yọrí sí ikú (g17.4 14)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Jem 1:17​—Kí nìdí tí Bíbélì fi pe Jèhófà ní “Baba àwọn ìmọ́lẹ̀ àtọ̀runwá”? (it-2 253-254)

    • Jem 2:8​—Kí ni “ọba òfin” náà? (it-2 222 ¶4)

    • Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. ) Jem 2:10-26 (th ẹ̀kọ́ 5)

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Ìpadàbẹ̀wò Kẹta: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ìwọ ni kó o yan ẹsẹ Ìwé Mímọ́ tó o máa lò. Pe ẹni náà wá sí ìpàdé. (th ẹ̀kọ́ 3)

  • Ìpadàbẹ̀wò Kẹta: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ìwọ ni kó o yan ẹsẹ Ìwé Mímọ́ tó o máa lò. Fi ọ̀kan nínú àwọn ìwé ìkẹ́kọ̀ọ́ lọ̀ ọ́. (th ẹ̀kọ́ 12)

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (5 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) bh 28-29 ¶4-5 (th ẹ̀kọ́ 13)

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 45

  • “Ẹ Máa Ronú Lórí Àwọn Nǹkan Yìí”: (8 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà, Yẹra fún Ohun Tó Lè Ba Ìdúróṣinṣin Rẹ Jẹ́—Eré Ìnàjú Tí Kò Bójú Mu.

  • Ẹ̀yin Òbí—Ẹ Kọ́ Àwọn Ọmọ Yín Kí Wọ́n Lè Yẹra fún Fífi Ọ̀rọ̀ Ìṣekúṣe Ránṣẹ́ Lórí Fóònù: (7 min.) Alàgbà ni kó sọ àsọyé yìí, a mú u jáde látinú Jí! January-February 2014 ojú ìwé 4 àti 5

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) bh orí 11 ¶1-6

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 130 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́