FEBRUARY 17-23
JẸ́NẸ́SÍSÌ 18-19
- Orin 1 àti Àdúrà 
- Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.) 
ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
- “‘Onídàájọ́ Gbogbo Ayé’ Pa Sódómù àti Gòmórà Run”: (10 min.) - Jẹ 18:23-25—Ọkàn Ábúráhámù balẹ̀ pé gbogbo ìgbà ni Jèhófà máa ń ṣe ìdájọ́ òdodo (w17.04 18 ¶1) 
- Jẹ 18:32—Jèhófà fi dá Ábúráhámù lójú pé òun ò ní pa ìlú Sódómù run tí òun bá rí olódodo mẹ́wàá níbẹ̀ (w18.08 30 ¶4) 
- Jẹ 19:24, 25—Jèhófà pa ìlú Sódómù àti Gòmórà run torí ìwà búburú wọn (w10 11/15 26 ¶12) 
 
- Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (10 min.) - Jẹ 18:1, 22—Ọ̀nà wo ni Jèhófà gbà “fara hàn” Ábúráhámù, tó sì tún “wà pẹ̀lú” rẹ̀? (w88 5/15 23 ¶4-5) 
- Jẹ 19:26—Kí nìdí tí ìyàwó Lọ́ọ̀tì fi di “ọwọ̀n iyọ̀”? (w19.06 20 ¶3) 
- Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì? 
 
- Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Jẹ 18:1-19 (th ẹ̀kọ́ 12) 
MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ
- Ìpadàbẹ̀wò Àkọ́kọ́—Fídíò: (5 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà, lẹ́yìn náà béèrè àwọn ìbéèrè yìí: Báwo ni akéde náà ṣe nasẹ̀ Ìwé Mímọ́ lọ́nà tó dára? Báwo ló ṣe jẹ́ kí onílé lóye ohun tó kà nínú ẹsẹ Bíbélì náà? 
- Ìpadàbẹ̀wò Àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. (th ẹ̀kọ́ 6) 
- Ìpadàbẹ̀wò Àkọ́kọ́: (5 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. Lẹ́yìn náà fún onílé ní ìwé Kí Ni Bíbélì Kọ́ Wa? kó o sì ṣàlàyé àwòrán tó wà lójú ìwé 98. (th ẹ̀kọ́ 9) 
MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI
- “Bó O Ṣe Lè Jàǹfààní Látinú Ṣíṣàyẹ̀wò Ìwé Mímọ́ Lójoojúmọ́”: (15 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà Ẹ Má Ṣe Máa Nífẹ̀ẹ́ Ayé (1Jo 2:15). 
- Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) bh orí 16 ¶1-8 
- Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) 
- Orin 2 àti Àdúrà