ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 July ojú ìwé 3
  • July 13-19

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • July 13-19
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 July ojú ìwé 3

July 13-19

Ẹ́KÍSÓDÙ 8-9

  • Orin 12 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Fáráò Agbéraga Ò Mọ̀ Pé Ohun Tí Jèhófà Fẹ́ Ni Òun Ń Ṣe”: (10 min.)

    • Ẹk 8:15​—Fáráò mú ọkàn rẹ̀ le, kò sì fetí sí Mósè àti Áárónì (it-2 1040-1041)

    • Ẹk 8:18, 19​—Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn àlùfáà onídán Íjíbítì ò lè ṣe ohun tí Mósè àti Áárónì ṣe, síbẹ̀ Fáráò ṣagídí.

    • Ẹk 9:15-17​—Kí Jèhófà lè ṣe orúkọ rẹ̀ lógo, ó dá ẹ̀mí Fáráò sí (it-2 1181 ¶3-5)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (10 min.)

    • Ẹk 8:21​—Kòkòrò wo ni eṣinṣin mùjẹ̀mùjẹ̀ náà? (it-1 878)

    • Ẹk 8:25-27​—Kí nìdí tí Mósè fi sọ pé “àwọn ará Íjíbítì máa kórìíra” ohun tí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì fẹ́ fi rúbọ? (w04 3/15 25 ¶10)

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ẹk 8:1-19 (th ẹ̀kọ́ 12)

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Fídíò Nígbà Àkọ́kọ́: (4 min.) Ìjíròrò. Ẹ wo fídíò náà, lẹ́yìn náà béèrè pé: Báwo ni akéde náà ṣe fèsì nígbà tí onílé yẹn ò fẹ́ gbọ́ ìwàásù? Kí ni akéde náà lè sọ tó bá fẹ́ fún onílé ní ọ̀kan lára àwọn ìtẹ̀jáde tó wà nínú Àpótí Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́?

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ. (th ẹ̀kọ́ 6)

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ. Onílé sọ ohun táwọn èèyàn sábà máa ń sọ ní ìpínlẹ̀ yín tí wọn kò bá fẹ́ gbọ́ ìwàásù. Fèsì ní ṣókí, kó o sì máa bá ọ̀rọ̀ rẹ lọ. (th ẹ̀kọ́ 3)

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ. Fi ọ̀kan nínú àwọn ìwé ìkẹ́kọ̀ọ́ lọ̀ ọ́. (th ẹ̀kọ́ 12)

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 74

  • “Jẹ́ Onírẹ̀lẹ̀​—Má Ṣe Máa Fọ́nnu”: (7 min.) Ìjíròrò. Ẹ wo fídíò náà Di Ọ̀rẹ́ Jèhófà​—Jẹ́ Onírẹ̀lẹ̀. Lẹ́yìn náà, tẹ́ ẹ bá láwọn ọmọdé, pe àwọn bíi mélòó kan wá sórí pèpéle, kó o sì bi wọ́n nípa fídíò náà.

  • “Jẹ́ Onírẹ̀lẹ̀ Táwọn Míì Bá Ń Yìn Ẹ́”: (8 min.) Ìjíròrò. Ẹ wo fídíò náà Jẹ́ Adúróṣinṣin Bíi Jésù​—Nígbà Tí Wọ́n Bá Ń Yìn Ọ́.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) jy orí 123 àti àpótí ojú ìwé 282

  • Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

  • Orin 44 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́