Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọkùnrin nìkan làwọn tá a mẹ́nu bà nínú àpilẹ̀kọ yìí, ọ̀pọ̀ àwọn obìnrin ló ń tiraka láti lè jáwọ́ nínú fífọwọ́ pa ẹ̀yà ìbímọ. Nítorí náà, tọkùnrin tobìnrin ni ìmọ̀ràn yìí wà fún. Tún rántí pé ohun tí àpilẹ̀kọ yìí dá lé ni fífọwọ́ pa ẹ̀yà ìbímọ ara ẹni. Fífọwọ́ pa ẹ̀yà ìbímọ ẹlòmíì tí kì í ṣe ẹni téèyàn bá ṣègbéyàwó wà lára ohun tí Bíbélì pè ní àgbèrè, ẹ̀ṣẹ̀ tó burú jáì lójú Ọlọ́run sì ni.—Wo àpilẹ̀kọ náà “Àwọn Ọ̀dọ́ Béèrè Pé . . . Kí Ló Burú Nínú Kéèyàn Ní Ìbálòpọ̀ Ṣáájú Ìgbéyàwó?” bó ṣe wà nínú ìtẹ̀jáde wa ti August 8, 2004, ojú ìwé 14 sí 16.