Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Àwọn Kristẹni ní ìdí tó ṣe gúnmọ́ tí wọn ò fi gbọ́dọ̀ máa pèdè tí ò dáa lẹ́nu, torí Bíbélì sọ pé: “Kí àsọjáde jíjẹrà má ti ẹnu yín jáde.” “Ẹ jẹ́ kí àsọjáde yín máa fìgbà gbogbo jẹ́ pẹ̀lú oore ọ̀fẹ́, tí a fi iyọ̀ dùn.”—Éfésù 4:29; Kólósè 4:6.