Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Bí wọ́n ṣe lo àwọn orúkọ Hébérù nínú àwọn ìran mìíràn ti ọ̀rọ̀ yìí lẹ́yìn; Jésù ni a fún ní orúkọ Hébérù náà “Ábádónì” (tí ó túmọ̀ sí “Ìparun”), tó sì máa mú ìdájọ́ ṣẹ ní kíkún ní ibì kan “tí a ń pè ní Ha-Mágẹ́dọ́nì lédè Hébérù.”—Ìṣípayá 9:11; 16:16.