ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

b Kí Jésù tó lè san ìràpadà tó ṣe rẹ́gí pẹ̀lú ohun tí Ádámù sọ nù, ó gbọ́dọ̀ jẹ́ ẹni pípé tó ti dàgbà nígbà tó bá máa kú, kì í ṣe ọmọ kékeré. Rántí pé ṣe ni Ádámù mọ̀ọ́mọ̀ dẹ́ṣẹ̀, ó mọ̀ pé ohun tóun ṣe ò dáa àti pé Jèhófà máa fìyà jẹ òun tóun bá ṣe é. Torí náà, kí Jésù tó lè di “Ádámù ìkẹyìn” kó sì bo ẹ̀ṣẹ̀ náà mọ́lẹ̀, ó ti ní láti dàgbà torí ìyẹn lá jẹ́ kó mọ ohun tó ń ṣe, kó sì pinnu pé òun máa jẹ́ adúróṣinṣin sí Jèhófà. (1 Kọ́ríńtì 15:45, 47) Nípa bẹ́ẹ̀, bí Jésù ṣe jẹ́ olóòótọ́ sí Jèhófà jálẹ̀ ìgbésí ayé ẹ̀ àti bó ṣe kú torí àwa èèyàn jẹ́ “ìwà òdodo kan.”​—Róòmù 5:18, 19.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́