Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Wòlíì Èlíṣà ti fún ìránṣẹ́ rẹ̀ nírú ìtọ́ni bẹ́ẹ̀ rí. Nígbà tó ń rán Géhásì ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ sílé obìnrin kan tí ọmọ rẹ̀ kú, Èlíṣà sọ pé: “Bí ó bá ṣẹlẹ̀ pé o bá ẹnikẹ́ni pàdé, ìwọ kò gbọ́dọ̀ kí i.” (2 Àwọn Ọba 4:29) Iṣẹ́ kánjúkánjú ni, kò sídìí láti fi àkókò ṣòfò.