ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

b Bíbélì fi hàn pé wíwulẹ̀ ní ẹ̀rí ọkàn tí kò dani láàmú ò tó. Bí àpẹẹrẹ, Pọ́ọ̀lù sọ pé: “Èmi kò ní ìmọ̀lára ohunkóhun lòdì sí ara mi. Síbẹ̀, nípa èyí, a kò fi mí hàn ní olódodo, ṣùgbọ́n ẹni tí ń wádìí mi wò ni Jèhófà.” (1 Kọ́ríńtì 4:4) Bíi ti Pọ́ọ̀lù, ẹ̀rí ọkàn àwọn tó ń ṣenúnibíni sáwa Kristẹni lè ṣàì dá wọn lẹ́bi torí wọ́n lè ronú pé ohun tínú Ọlọ́run dùn sí làwọn ń ṣe. Nítorí náà, ó ṣe pàtàkì ká ní ẹ̀rí ọkàn tó mọ́ lójú Ọlọ́run, kó má sì da àwa fúnra wa láàmú.—Ìṣe 23:1; 2 Tímótì 1:3.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́