Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Aṣọ náà lè jẹ́ aṣọ tí Pọ́ọ̀lù máa ń so mọ́ orí kí òógùn má bàa ṣàn wọnú ojú ẹ̀. Bí Pọ́ọ̀lù ṣe wọ épírọ́ọ̀nù lákòókò yìí fi hàn pé ó ṣeé ṣe kó máa ṣe iṣẹ́ àgọ́ pípa lọ́wọ́ àárọ̀, nígbà tọ́wọ́ ẹ̀ bá dilẹ̀, kó lè rí owó táá fi gbọ́ bùkátà ara ẹ̀.—Ìṣe 20:34, 35.