ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

a Ìwé Mímọ́ sọ nínú Jẹ́nẹ́sísì 2:10-14 pé: “Odò kan wà tí ń ṣàn jáde láti Édẹ́nì láti bomi rin ọgbà náà, ibẹ̀ ni ó sì ti bẹ̀rẹ̀ sí pínyà, ó sì di ohun tí a lè pè ní ẹ̀ka mẹ́rin. Orúkọ èyí èkíní ni Píṣónì . . . Orúkọ odò kejì sì ni Gíhónì . . . Orúkọ odò kẹta sì ni Hídẹ́kẹ́lì [tàbí Tígírísì]; òun ni èyí tí ó lọ sí ìlà-oòrùn Ásíríà. Odò kẹrin sì ni Yúfírétì.” Ní òde òní kò sí èèyàn tó mọ odó tó ń jẹ́ Píṣónì àti èyí tó ń jẹ́ Gíhónì, kò sì sí ẹni tó mọ ojú ibi tí odò méjèèjì yìí wà.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́