ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

b Èrò àwọn kan lára àwọn tó ń ṣàlàyé Bíbélì ni pé ohun tó dáa ni gbólóhùn yẹn gbé yọ, wọ́n ní tipẹ́tipẹ́ ni bí àwọn èèyàn ṣe ń kó iyọ̀ kí wọ́n lè fi máa pa nǹkan mọ́ ti ń mú èrè gọbọi wá fáwọn oníṣòwò tó wà ní agbègbè Òkun Òkú. Àmọ́ ẹ kíyè sí i pé, apá tá a tọ́ka sí nínú Ìwé Mímọ́ sọ pé àwọn ibi ẹrẹ̀ náà “kò . . . ní rí ìwòsàn.” Wọ́n á wà láìlẹ́mìí, wọn ò ní ṣeé wò sàn, torí omi ìyè tó ń ṣàn jáde láti ilẹ̀ Jèhófà kò ṣàn dé ọ̀dọ̀ wọn. Torí náà, ó dà bíi pé pẹ̀lú bọ́rọ̀ ṣe rí yìí, ohun tí kò dáa ni àwọn iyọ̀ tó wà níbi ẹrẹ̀ yẹn ń tọ́ka sí.​—Sm. 107:​33, 34; Jer. 17:6.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́