Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Èyí ni a mú ṣe kedere lẹ́yìn náà nígbà tí Satani sọ nípa Jobu, ìránṣẹ́ Ọlọrun náà pé: “Awọ fún awọ; àní ohun gbogbo tí ènìyàn ní, òun ni yóò fi ra ẹ̀mí rẹ̀. Ṣùgbọ́n nawọ́ rẹ nísinsìnyí, kí o sì fi tọ́ egungun rẹ̀ àti ara rẹ̀, bí kì yóò sì bọ́hùn ní ojú rẹ.”—Jobu 2:4, 5.