ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

b Jálẹ̀ Ìwé Mímọ́ Lédè Heberu, àwọn ọkùnrin àti obìnrin tí wọ́n ti lọ́kọ tí wọ́n sì ti láya ni a tọ́ka sí ní ọ̀pọ̀ ìgbà gẹ́gẹ́ bí “ọkọ” (Heberu, ʼish) àti “aya” (Heberu, ʼish·shahʹ). Fún àpẹẹrẹ, ní Edeni, ọ̀rọ̀ náà tí Jehofa lò, kì í ṣe “olówó” àti ‘ẹni tí a ni,’ ṣùgbọ́n “ọkọ” àti “aya.” (Genesisi 2:24; 3:16, 17) Àsọtẹ́lẹ̀ Hosea sọ pé lẹ́yìn pípadà dé láti oko-òǹdè, Israeli yóò fi ìrònúpìwàdà pe Jehofa ní “Ọkọ mi,” kì í sì ṣe “Olówó mi” mọ́. Èyí lè dámọ̀ràn pé ọ̀rọ̀ náà “ọkọ” ní ìgbéyọsọ́kàn oníjẹ̀lẹ́ńkẹ́ ju “olówó” lọ.—Hosea 2:16, NW.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́