Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ó kéré tán, nínú ọ̀ràn kan, ìyẹn ní ti Òfin Mẹ́wàá, “ìka Ọlọ́run” fúnra rẹ̀ ni ó fi kọ ìsọfúnni náà. Mósè wulẹ̀ ṣàdàkọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyẹn sínú àkájọ ìwé àti àwọn ohun ìkọ̀wé mìíràn ni.—Ẹ́kísódù 31:18; Diutarónómì 10:1-5.
a Ó kéré tán, nínú ọ̀ràn kan, ìyẹn ní ti Òfin Mẹ́wàá, “ìka Ọlọ́run” fúnra rẹ̀ ni ó fi kọ ìsọfúnni náà. Mósè wulẹ̀ ṣàdàkọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyẹn sínú àkájọ ìwé àti àwọn ohun ìkọ̀wé mìíràn ni.—Ẹ́kísódù 31:18; Diutarónómì 10:1-5.