b Ní ọjọ́ Jésù, kì í ṣe ibi ibùwọ̀ nìkan ni àwọn ilé èrò máa ń pèsè, ṣùgbọ́n wọ́n tún ń pèsè oúnjẹ àti àwọn nǹkan mìíràn. Ó lè jẹ́ irú ibùwọ̀ yìí ni Jésù ní lọ́kàn, nítorí ọ̀rọ̀ Gíríìkì tí a lò níhìn-ín yàtọ̀ sí èyí tí a lò fún “yàrá ibùwọ̀” nínú Lúùkù 2:7.