Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Lẹ́yìn tí wọ́n tẹ ọ̀rọ̀ ìbanilórúkọjẹ́ yẹn jáde nínú ìwé ìròyìn Rọ́ṣíà náà (tí a mẹ́nu kàn ní ìpínrọ̀ 15), Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ké gbàjarè sí Ìgbìmọ̀ Amójútó Ọ̀ràn Ìdájọ́ Tí Ń Rí sí Àríyànjiyàn Nípa Ìròyìn ní Ilẹ̀ Rọ́ṣíà, pé kí wọ́n dákun ṣàgbéyẹ̀wò àwọn ẹ̀sùn èké tí àpilẹ̀kọ náà gbé jáde. Lẹ́nu àìpẹ́ yìí, ilé ẹjọ́ náà gbé ìpinnu kan jáde tó na ìwé ìròyìn náà lẹ́gba ọ̀rọ̀ fún títẹ irú àpilẹ̀kọ burúkú bẹ́ẹ̀.—Wo Ji!, December 8, 1988, ojú ìwé 26 sí 27.