ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

b Ohun ìríra ni nǹkan wọ̀nyí jẹ́ sí Jèhófà fúnra rẹ̀. Fún àpẹẹrẹ, Éfésù 4:29 pe ọ̀rọ̀ ìríra ní “àsọjáde jíjẹrà.” Ọ̀rọ̀ Gíríìkì tá a lò fún “jíjẹrà” ń tọ́ka ní tààràtà sí èso, ẹja, tàbí ẹran tó ti rà. Irú ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ ń ṣàgbéyọ bí ọ̀rọ̀ èébú tàbí ọ̀rọ̀ àlùfààṣá ṣe gbọ́dọ̀ kó wa nírìíra. Bákan náà, a sábà máa ń pe àwọn òrìṣà ní “ẹlẹ́bọ́tọ” nínú Ìwé Mímọ́. (Diutarónómì 29:17; Ìsíkíẹ́lì 6:9) Bá a ṣe máa ń sá fún ẹlẹ́bọ́tọ, tàbí ìgbẹ́, ràn wá lọ́wọ́ láti lóye bí irú ìbọ̀rìṣà èyíkéyìí ṣe máa kó Ọlọ́run nírìíra tó.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́