Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ohun tó ṣẹlẹ̀ yẹn jọ ìgbà tí Rèbékà tó jẹ́ ìyá Jékọ́bù fún àwọn ràkúnmí Élíésérì lómi. Nígbà yẹn náà, Rèbékà sáré lọ sọ nílé pé àlejò kan ti dé. Bí Lábánì ṣe rí àwọn ohun èlò wúrà tí wọ́n fún arábìnrin rẹ̀, kíá ló sáré lọ pàdé Élíésérì.—Jẹ́nẹ́sísì 24:28-31, 53.