Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Nígbà tí Bíbélì bá lo gbólóhùn náà “àwọn olórí àlùfáà,” àwọn tó ń tọ́ka sí ni, àwọn àlùfáà àgbà àná, ẹni tó jẹ́ àlùfáà àgbà lọ́wọ́lọ́wọ́ àtàwọn tó wá látinú ìdílé tí ipò ńlá tọ́ sí lágbo àwọn àlùfáà.—Mátíù 21:23.
b Nígbà tí Bíbélì bá lo gbólóhùn náà “àwọn olórí àlùfáà,” àwọn tó ń tọ́ka sí ni, àwọn àlùfáà àgbà àná, ẹni tó jẹ́ àlùfáà àgbà lọ́wọ́lọ́wọ́ àtàwọn tó wá látinú ìdílé tí ipò ńlá tọ́ sí lágbo àwọn àlùfáà.—Mátíù 21:23.