Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Bó ṣe jẹ́ pé ìta làwọn olùṣọ́ àgùntàn ti ń tọ́jú àgbo ẹran wọn ní àkókò yìí jẹ́ ká rí i pé òótọ́ ni ìṣírò ọjọ́ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ inú Bíbélì: Oṣù December kọ́ ni wọ́n bí Kristi torí ìtòsí ilé ni wọ́n ti máa ń tọ́jú agbo ẹran wọn lásìkò yẹn, kàkà bẹ́ẹ̀, nǹkan bí ìbẹ̀rẹ̀ oṣù October ni wọ́n bí i.